a
Mk 9.30-32
;
Lk 9.43-45
;
Mt 16.21
;
20.17-19
;
26.2
.
Matthew 17:22-23
22
a
Nígbà tí wọ́n sì ti wà ní Galili, Jesu sọ fún wọn pé,
“Láìpẹ́ yìí a ó fi Ọmọ ènìyàn lé àwọn ènìyàn lọ́wọ́.
23
Wọn yóò sì pa á, ní ọjọ́ kẹta lẹ́yìn èyí, yóò sì jí dìde sí ìyè.”
Ọkàn àwọn Ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì kún fún ìbànújẹ́ gidigidi.
Copyright information for
YorBMYO